Ẹgbẹ ọmọ Yorùbá kí Gomina Abiola Ajimobi kú oríire ọjọ́ ìbí
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan, Central Council of Ibadan Indigenes(CCII) n ṣe akanṣe eto igbalejo fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mọkandinlaadọrin ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi.









Ile isẹ iroyin BBC lo ni awọn aworan yii.








