BBNaija: Khafi la Mercy àti Cindi mọ́lẹ̀ nínú abala tó kẹ́yìn ìdíje ọ̀rọ̀ nípa Nàíjíríà

Oríṣun àwòrán, Instagram/khafikareeem
Khafi Kareem to jẹ ọkan lara awọn to n kopa ninu eto agbelewo kan, Big Brother Nigeria, taa mọ si BBNaija ti gba ẹbun ọkọ ayọkẹlẹ lori eto naa.
Khafi to jẹ ọlọpaa nilẹ Gẹẹsi sọrọ loju opo Instagram rẹ pe, oun lẹni to ṣẹṣẹ ni ọkọ tuntun nigboro bayii.
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post, 1
Khafi jẹ ẹbun ọkọ ti ileeṣẹ to n ṣe mọto, Innoson Motors gbe kalẹ fun ẹni to ba gba ipo kinni, ninu idije sisọ ọrọ lori bi orilẹede Naijiria ṣe n wu wọn lori to.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn
- Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham
- Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji
- Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka
- Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà si Nàìjíríà láti India
Khafi ni wọn lo sọrọ iwuri nipa Naijiria julọ, lẹyin naa ni wọn kede rẹ gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idije naa.

Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi
Ni abala akọkọ, gbogbo oludije to wa nile lo sọrọ lọpọlọpọ nipa Naijiria, amọ Khafi, Mercy, Cindy ati Jackye nikan lo pegede de abala to kẹyin.
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post, 2
Mercy, Cindy ati Jackye ja fitafita lati moke ninu abala to kẹyin, ṣugbọn Khafi la gbogbo wọn mọ lẹ.
Ni ọsẹ to lọ niroyin sọ pe, ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi n ṣewadii fọnran kan lori ayelujara eyi ti ọpọ gbagbọ pe Khafi n ni ibalopọ pẹlu akẹgbẹ rẹ, Gedoni ninu rẹ.
- Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka
- Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin
- Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji
- Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun
- Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson
Koda iroyin naa ni Khafi le padanu iṣẹ lori ọrọ naa nitori iwa ibanilorukọ jẹ lo jẹ ati pe ileeṣẹ ọlọpaa ko fun laye lati lọ kopa ninu idije BB Naija.























