Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ọ̀lù ní Afíríkà yẹ́ Gomina Ambode si

Akinwumi Ambode

Oríṣun àwòrán, Akinwumi Ambode

Àkọlé àwòrán, Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ ọ̀lù lágbàyé yẹ́ Gomina Ambode si
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1

Ọ̀pọ̀ àwọn àgbà sjẹ̀ oníbọọ̀lù láti orilẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Afíríkà ló péju sí pápá ìṣere Agege lọ́nìí láti yẹ gọmina ìpínll Eko Akinwumi Ambode bí ó ṣé ń fi ìpò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bii gómìnà.

Awọn ènìyàn bi George Weah to jẹ ààrẹ orilẹ̀-èdè Liberia, Eto'o, Toure lo yẹ ko peju sibi ayẹyẹ ohun.

Àkọlé fídíò, 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'

Nínú ọ̀rọ̀ ìdúpẹ̀ rẹ̀ gómìnà Akinwumi Ambode ni inú òhun dùn gidigidi bí àwọn agbábọ̀ọ̀lù náà ṣe ṣe àyẹ́sí fún òhún, o ni àwọn dájọ, ọjọ́ náà sikò àti pe òun dupẹ lọ́wọ́ àwọn to ṣe àgbátẹrùn ètò náà àti gbogbo àwọn to wá si pápá ìṣèré náà láti wa wòran

Awon ololufe boolu

Oríṣun àwòrán, AkinwumiAmbode

Àkọlé àwòrán, Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ ọ̀lù lágbàyé yẹ́ Gomina Ambode si

Awọn olólùfẹ́ gómìnà Akinwumi Ambode náà ko gbéyin lóri àtẹjiṣẹ́ twitter láti fi ìdùnú wọn han lórí ìfẹsẹwọnsẹ náà.

Skip X post
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post