You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
A kò mọ irú èpè tí a lè ṣẹ́ fún awakọ̀ tó pa ẹbí Fatinoye mọ́ ṣùgbọ́n....ẹbi Kehinde àti Bukola Fatinoye
Pẹ̀lú ìbànujẹ́ àti arò ni ẹbi Fatinoye ṣe n sọ̀rs nípa tọkọtayà onínúre Bukola àti Kehinde Fatinoye.
Sẹ ẹ ranti tọkọtaya Fatinoye ni ilu Abeokuta nipinlẹ Ogun ni Guusu Naijiria ti ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria kede pe awakọ wọn, Lekan ti jẹwọ pe oun lo seku pa wọn.
Lorumọju ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2023 yii léyin eto isinonigbagbọ aisun ọdun tuntun ni iṣẹlẹ iabnujẹ yii waye ninu ile tọkọtaya naa nilu Abeokuta.
- “Ẹ̀ṣẹ̀ Lekan, awakọ̀ Fatinoye ju tí Judasi lọ, gbogbo ẹbí ló dá lóró”
- Ọkùnrin méjì tó rà mọ́tò Fatinoye bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá
- Ìdí tí a fi mú 'girlfriend' Lekan, ìyà rẹ̀ àti Lekan náà mọ́ àwọn ọ̀daràn rèé- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá
- N2.1m ni ọ̀gá mi ‘transfer’ sí wa lójú ìbọn, ká tó jó òun àti aya rẹ̀ mọ́lé - Awakọ̀
- Morenikeji Lasisi, 'Baba Kekere' olórí ẹrú Ọba Alaafin Oyo ti jáde láyé
- Mọ̀ síi nípa ewu tó rọ̀ mọ́ níní ìbálòpọ̀ lásìkò ìlóyún lórí ètò Sé lóòtọ́ ní BBC
Pẹlu ibanujẹ ni awọn eeyan ṣe n sọrọ niap arabinrin Bukola ati arakunrin Kehinde Fatinoye pẹlu ọmọ wọn Ore oluwa ti awọn oniṣẹ ibi ṣekupa nipinlẹ Ogun.
Oṣiṣe banki Naijiri ani ọkọ nigba ti iyawo rẹ jẹ oṣiṣẹ Fasiti olohun ọgbin ni Abeokuta nipinlẹ Ogun.
Ogbeni Akinkunmi Jiboku, Rasheed Fajinmi, Zacheaus Fatinoye, Micheal Fatinoye, Sani Ogundele, ṣapejuwe tọkọtay naa ni oniwa tutu to jẹ ọmọluwabi eniyan.
Awọn miran to tunwa nibi eto isin idagbere to waye fun tokotyaya naa tun ṣapejuwe wọn pe ọmọluwabi ẹda ti awọn eeyan maa mọ riri wọn ni wọn jẹ.
Koda, ọpọ sọ pe awọn ko mọ iru epe ti awọn yoo tun ṣe fun Lekan to jẹ awakọ to ṣeku pa awọn oninure naa tọmọtọmọ.
- Èèyàn 44,000 pàdánù ẹ̀mí wọn lápapọ̀; ilé 345,000 ló dàwó nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ rírì ní Turkey
- Ètò ìdìbò 2023, àjọ FRSC yọ̀nda òṣìṣẹ́ 21,783 láti ṣerànwọ́ lásìkò ìdìbò
- Ó kéré tán, ogún ọkùnrin ló n bá mi sùn lójúmọ́- Adenike Olanipekun
- 'Irọ́ ni! EFCC kò bá N400billion nílé Tinubu'
- Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà