Aláànú àti Olùfọkànsìn ní tókótaya Kehinde àti Bukola Fatinoye- Alufaa S K Oyewale

Gbogbo eeyan ni à\won tọkọtaya yii n ran lọwọ lai ni igberaga- Alufaa ijọ wọn.Àwọn oníṣẹ́ ibi tó pa tọkọtaya náà de àwa tí a kọ́kọ́ dé síbẹ̀ mọ́lẹ̀- Ó ṣojú mi

BBC Yoruba ti wa Alufaa agba ijọ ti tokotaya Fayinoye n lo ni Iporo Ake ni ilu Abeokuta, ni ipinle Ogun to wa ni iwo oorun guusu Naijiria kan.Wọn ti rí òku Ooreoluwa, ọmọ tọkọtaya tí wọ́n dáná sún ni Abeokuta lọ́jọ́ ọdún, wo ohun tí ọlọ́pàá Ogun tún sọ..-

Al;ufaa agba S. Kolawole Oyewale to n dari ijọ Christ Anglican Church ni Iporo Ake ni Abeokuta ṣalaye iru eeya ti tọkọtaya Kehinde ati Olubukola Fatinoye jẹ fun BBC pe Aláànú àti Olùfọkànsìn ní tókótaya Kehinde àti Bukola Fatinoye.

Bakan naa lo sọ nipa asiko igbẹyin awọn oloogbe naa ninu ijọ lasiko isin ọdun tuntun naa.

O tun fi igabgbọ rẹ han leyin iku pe wọn ti lọ sinmi laya Olugbala wọn bayii.

Kini olopaa sọ bayii?

Oga ọlọpaa Abimbola Oyeyemi ti o je alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun naa ti ba BBC Yoruba sọrọ lori iṣẹlẹ buruku yi.

O ni ohun ibanujẹ ni.

Oyeyemi ṣalaye bi wọn se ri oku ọmọ awọn tokotaya yii ati bi wọn se ri ẹnikan to n ba won gbe.

Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ afurasí kan lórí ìṣekúpa tọkọtaya tí wọ́n dáná sun ni Abeokuta- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàáá

Alábàgbé tọkọtaya ti wọ́n pa ní Ogun wà láàyè, ó wà ní ìpamọ́, ìwádìí n lọ lọ́wa báyìí- Oyeyemi Sgá ọlọ́pàá Ogun.