The9jaboy: Ojú burúkú ni wọ́n fi ń wo ìwé ìrìnnà aláwọ́ ewé Nàìjíríà nílẹ̀ òkèèrè- MCDolly Ogundana
Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà ẹ jẹ ki a jẹ aṣoju rere kaakirir agbaye nitori iwe irinna ọwọ wa.
Ogbeni McDolly Ogundana to jẹ arinrinajo kaakiri agbaye sọ bo ṣe bẹrẹ irinajo naa ati ibi ti ọrọ irinajo rẹ de duro kaakiri agbaye fun BBC Yoruba.
O menuba bo ṣe lọ si awọn orilẹ-ede ni North America, Africa, Asia ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Bakan naa lo tun sọ nipa awọn ipenija to ri ati ipa to fẹ fi lelẹ lẹyin Ajala Travel to jẹ ogbontarigi arinrinajo ni Naijiria.
- Àwọn nọ́ọ̀sì ní UK gùn lé ìyanṣẹ́lódì, pè fún ẹ̀kúnwó
- Èèyàn mẹ́rin farapa yánayàna níbi òde orin Asake nílùú London-
- Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ
- Mo kọ̀ láti fí owó kó aya jọ ní mo ṣe lọ káwé láti LLB dé PhD ǹsìyìí lárúgbọ ara- Oba Ogunleye
- 'Ayé kọ́ ló ṣe mi tí ojú fi fọ́, àmọ́ bí mo ṣe ń fi ojú tó fọ lu gangan, tún -generator- ṣe kò yé mi'
- Iṣẹ́ òpùrọ́ ni Olọ́run fi rán APC, wọn kò ṣiṣẹ́ ìlú kankan ní Kwara- Bolaji Abdullahi