You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Ọkùnrin kan ṣe ìgbéyàwó fún obìnrin mẹ́rin lọ́jọ́ kan náà
Ọkunrin oniṣowo kan ti di gbajumọ lori ayelujara lẹyin to ṣe igbeyawo pẹlu obinrin mẹrin lọjọ kan naa.
Oniṣowo ọhun ti orukẹ rẹ n jẹ Mesmine Abeeole ṣe igbeyawo pẹlu awọn obinrin naa lagbegbe Libreville, lorilẹ-ede Gabon.
Iroyin kede orukọ awọn aya ọkunrin ọhun bii Madeleine Nguema, Prisca Nguema, Nicole Mboungou ati Carene Sylvana Aboghet.
- A ti mú afurasí darandaran méjì tó ń da màálù tó kan ọmọ oṣù mẹ́ta pa- Ọlọ́pàá
- Òjò àrọ̀rọ̀dá gbẹ̀mí èèyàn mẹ́ta ní Oshogbo,ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò
- Ẹbí Rachael Oniga kéde ètò ìsìnkú òṣèré tó d'olóògbé
- Ìjọba Eko jáwọ́ nínú ẹ̀sùn tó fi kan Ọba Ogboni pé ó pààyàn ní ìwọ́de Yoruba Nation ní Ojota
- Afẹnifẹre kan sárá sí ẹ̀ka ètò ìdájọ́ Nàìjíríà lórí ìdájọ àwọn ti wọ́n kó nílé Sunday Igboho
Ọpọ awọn eeyan kaakiri agbaye lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori igbeyawo naa lẹyin ti awọran wọn jade lori ayelujara.
Diẹ lara awọn aworan igbeyawo naa ree: