Iba Lassa: Wo awọn ọna ti o le gba dena arun naa

Oríṣun àwòrán, AFP
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1
Lorilẹede Naijiria awọn eniyan ti o ti padanu ẹmi wọn sọwọ iba rẹrẹ ti le ni ogun ninu odun 2018, gẹgẹ bi ajọ ti o n se amojuto arun se so.
Ipinlẹ mẹtala ni iba yi ti sẹyọ lọwọlọwọ, sugbọn awọn ona ti o rọrun wa ti a le gba dena rẹ - wo fọnran BBC Yoruba yi lori ikanni Facebook fun awọn ona naa.



















