You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùbá
O tó gẹ́, kí a kó apá tí kò bá ṣe é ṣán mọ́ padà sórí ni Nàìjíríà- Oyinlola
Gomina ipinlẹ Osun nigba kan ri, Oloye Olagunsoye Oyinlola gba BBC Yoruba lalejo, O sọrọ ilẹ kun lori ibi ti Naijiria de duro
Oyinlọla fi ẹdsun ọkan rẹ han lori bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe yi ohun pada lori ọrọ 'Restructuring' ti gbogbo wọn fi ta Buhari fun Yoruba lasiko idibo.
O ni o dun oun pe Buhari ni pe oun ko mọ nkan to n jẹ 'Restructuring'mọ nisinyi.
- Bí ọkọ mi ṣe fi ẹ̀wọ̀n irin dè mí mọ́ bẹ́ẹ̀dí tó fipà bá mi lòpọ̀ títí oyún fi bàjẹ́ lára mi'
- Ìdí tí mo fi jú ọmọ mi ọmọ ọdún méjì látorí ilé gogoro sílẹ̀
- A ti gba ẹ̀sùn tí ẹ fi kan Buhari, Malami, Buratai wọlé - Kóótù `ọdaràn l'ágbáyè, ICC
- Wọ́n ní Ìyá Esabod yẹn ma ń ṣépè, fi òṣèré wọ́lẹ̀, mò ń retí èsì yín sí ọ̀rọ̀ tí mo fi síta yìí - Mr Portable
Oyinlọla gbadura idariji nitori pé ko si ootọ mọ.
O ni Oun mọ ọpọlọpọ ipa ti oun ko ninu igbesẹ to sọ Buhari di aarẹ Naijiria ṣugbọn pẹlu ibanujẹ ni o fi han pe wọn ko mu ikankan ṣẹ ninu ileri to pọ ti wọn ṣe paapaa lori eto aabo.
Olagunsoye ni ohun to fi dabi pe Boko Haram yoo dohun igbagbe laarin oṣu mẹfa ti Buhari ba de ibẹ tẹlẹ ni.
- Ìròyìn òfegè ni pé Alabi Yellow jáde láyé lánàá
- Wo ìgbésẹ̀ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ń gbé lẹ̀yìn tí wọ́n rí ẹ̀dà Covid-19 "Delta variant" tuntun níbẹ̀
- Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ Adelere Oriolowo, APC tó fi opó ẹ̀rọ ayélujára Airtel ṣe iṣẹ́ àkànṣe ìlú ní Osun
- Àrá kọ ṣàràà! Ó sán pa èèyan 16 tó ń ya "Selfie" lórí ilé gogoro
- 'Surprise Cake' tí mo gbà lọ́jọ́ ìbí mi ní kò jẹ́ kí ń pa ara mi- Deborah Oyesanya
Olusegun Obasanjọ kìlọ̀ fún wa pé Buhari kò lè gbé ẹrù Nàìjíríà ṣùgbọ́n a kò gbọ́ sí i lẹ́nu- Olagunsoye Oyinlola.
O to gẹ, ti apa ko ba ṣe e ṣan mọ, eeyan maa n kaa lori ni ibi ti ọrọ Naijiria de duro bayii.
Asiko ti to ki a pada si bo ṣe wa tẹlẹ laye Awolowọ ti onikaluku n mojuto ẹkun rẹ ni.
Eto ẹkọ, eto ọgbin, ile gbigbe, ọna ṣiṣe ati bẹẹ bẹe lọ ni koowa n mojuto bo ṣe wu u.
Ti iwájú kò bá ṣe é lọ, kí a kúkú padà síbi tí a ti bẹ̀rẹ̀- Olagunsoye Oyinlola
Bẹẹ ko sẹni ti a le maa bẹ pe ko maa ṣẹru nigba gbogbo nigba ti a ko pin nkan bi o ṣe yẹ.
- Wo aya tuntun tí Balogun Super Eagles, Ahmed Musa fẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìyàwó kẹta
- Ẹ fọkàn balẹ̀, Wakili ò gbèrò láti ṣe ìkọlù sí Igangan àti Ibarapa lọ́jọ́ Ileya- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo
- Wo ìlú kan ní Italy tó ṣetán láti fún ọ ní N13.6 mílíọ̀nù tí o bá gbà láti gbé níbẹ̀
- Ìròyìn òfegè ni pé Alabi Yellow jáde láyé lánàá
- Àrá kọ ṣàràà! Ó sán pa èèyan 16 tó ń ya "Selfie" lórí ilé gogoro
- Wọ́n ti yọ ojú òpó 'GoFundMe' tí wọ́n ṣí fún Baba Ijesha ní Ireland kúrò lórí ayélujára