Coronavirus in Nigeria: Ayodeji Osowobi ṣàlàyé bí ó ti jàjà bọ́ lọ́wọ́ àrùn covid-19

Àkọlé fídíò, Eniyan mẹfa lo ti ku nitori arun Coronavirus yii lorileede Naijiria.

Arun Coronavirus ti pa ẹgbẹgbẹrun eniyan kaakiri agbaye, ti o si ti sọ ọpọ di alailara.

Amọ bi arun naa ṣe buru to, awọn eniyan miran ṣi n ru ye, ti wọn si n sọ iriri wọn.

Lara wọn ni arabinrin Ayodeji Osowobi to ko arun Coronavirus, to si ri iwosan gba lorilẹede Naijiria.

Ẹ gbọ iriri rẹ: