Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Aarẹ Bola Tinubu ti paṣẹ igbedide ẹṣọ aṣọbode lorilẹ ede kọọkan to w ani ECOWAS
lati wo gbogbo igbegidina to wa laarin awọn orilẹede naa
lojuna ati mu igbokegbodo, awọn araalu ati okoowo maa lọ ni irọwọrọsẹ
Aṣoju Naijiria ni ECOWAS, Musa Nuhu sọ awọn ti bẹrẹ pẹlu ẹnubode Seme ati Badagry
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx
Ọdọmọbinrin kan, Helen Kayode ti ko si gbaga ọlọpaa ni Ekiti
Fẹsun pe o parọ pe awọn agbebọn kan ji oun gbe
Ti wọn si ti oun mọ ile kan loju ọna Iworoko si Ado-Ekiti
Amọ agbẹnusọ ileesẹ ọlọpaa Ekiti, Sunday Abutu sọ pe ile ọkunrin ni Helen wa lorumọju ọjọ naa
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx
Njẹ o mọ pe obinrin ti de ipo poopu ri?
Irọ ni o!
Iroyin ni sẹnturi kẹsan-an ni Obinrin Joan pa orúkọ dà di John tó si darí ìjọ Àgùdà pẹ̀lú orúkọ Póòpù John VIII
Ki aṣiri to tu pé John tó ń jẹ́ kìí ṣe John ọkùnrin bíkòṣe Joan
Bawo wa laṣiri ṣe tu?
Fun ẹkunrẹrẹ
