Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àkójọpọ̀ àwọn ìròyìn káàkiri Nàìjíríà tí kò ṣe é má gbọ̀ ọ́.
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Awuwuye lori aba ofin owo ori tuntun ni Naijiria

Kekere kọ, duro na, ṣe gbogbo awọn ọlọja kekeke naa yoo maa sanwo ori bayii?

Rara o, ẹnikẹni ti owo to n ri ko ba to miliọnu kan NAIRA lọdun kan lọdun ko ni sanwo ori o

Ma laagun jina, lo sori ikanni BBC Yoruba fun alaye kikun lori ọrọ naa

Ori lo mọṣẹ aṣela lo difa fun akẹkọọgboye fasiti to n kiri mọin-mọin

Ko lo n sọ lẹnu ti o dun yii, nibo lẹni naa wa?

Arakunrin kan Gideon Kupolati akẹkọọ gboye fasiti ilu Ilorin lo sọ fun BBC Yoruba pe

ipele kẹta loun wa lẹnu eto ẹkọ oun nigba toun bẹrẹ si ni fi kootu kiri mọin-mọin

Ko lo sun debẹ gan-an?

Kan soju opo BBC Yoruba fun ẹkunrẹrẹ

Aṣe loootọ ni pe ko si ohun t’ọkunrin le ṣe t’obinrin o le ṣe

Bẹẹ nio, Arabinrin Netumbo Nandi-Ndaitwah ti di aarẹ obinrin akọkọ orilẹede Namibia

Lẹyin iburawọle rẹ, Nandi-Ndaitwah yoo di Aarẹ obinrin keji nilẹ adulawọ lẹyin

Aarẹ Samia Suluhu Hassan Tanzania