You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Ramadan Fast 2021: Pásítọ̀ pín ounjẹ iṣínu àwẹ̀ fún àwọn Músùlùmí
Bísọ̀ọ̀bù àgbà nígbà kan rí nílùú Abuja, John Onaiyekan tí pín ounjẹ́ tó lé ni igba fún àwọn músùlùmí bí ẹgbẹ̀rún méjì ní mọ́sálásí Al-Habibiyah ní agbègbè Guzape nìlùú Abuja tíí ṣe olúùlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Lásìkò tí wọ́n péjọ láti ṣinu ààwẹ̀ ní òun àti àwọn onígbàgbọ́ míírà sàbẹ̀wò sí mọ́sálásí náà.
Ilé iṣẹ́ ìròyìn Channels gbé àwọn fótò bí Bísọ̀ọ̀bù àgbà ọ̀ún ṣe ń pín ounjẹ náà fún àwọn mùsùlùmí láti ṣínu.
- Àwọn aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ EKSU ti ní kí wọ́n gbé ilé ẹ̀kọ́ náà tì pa!
- Àtẹ̀jádé ìjọba apapọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pantami fihàn pé wọ́n ń káànú ìgbésùnmọ̀nmí- PDP
- Àwọn aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ EKSU ti ní kí wọ́n gbé ilé ẹ̀kọ́ náà tì pa!
- Màálù tí Ojo fẹ́ fi ṣègbeyàwó ló fẹ́ lọ rà tí wọ́n fi pà á, ti wọ́n gé ẹ̀yà ara rẹ̀ ní Kwara
- Àwọn Olùkọ́ Yorùbá ní ìpínlẹ̀ Osun ṣe bẹbẹ lórí ètò Akomọlede àti Aṣa lórí BBC
- Ẹjọ́ ń bẹ lọ́run fún gbogbo ẹ̀yin tí kò wàásù fáwọn tó ń tẹ lé yín lórí Instagram àti Facebook- Mike Bamiloye
Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ lásìkò tó n pín, ó ṣàlàyé pé Ọlọ́rùn fẹ́ràn kí krìstẹ́nì fi ìfẹ́ hán nítòrí ìfẹ́ ni òun fúnra rẹ̀, àti pé àwọn ń ṣe èyí láti jẹ́ kí àláfíà kó jọba láàárín krìsẹ́ní àti Musulumi.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Imaamu Mọ́sálásí Al- Habibyyah Fuad Adeyemi sọ pé, ǹkan tí adarí krìtẹ́nì ṣe yìí fi hàn pé ẹ̀sìn méjèèjì lé jọ́ jùmọ̀ gbé pọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rẹ́ àti ni ìgbé àlàfíà.
- Olólùfẹ́ Naira Marley kọ sẹ́nu tírélà nítorí ₦500 tó fẹ́ gbà lọ́wọ́ rẹ̀
- Mo fẹ́ ìyàwó méjì lọ́jọ́ kan ṣoṣo láti ṣe ju ohun tí bàbá mi gbé ṣe - Uloho Othuko
- Àwọn alákòso BCOS tan ìmọ́lẹ̀ sí ọ̀rọ̀ iléègbé àwọn òṣíṣẹ́ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo bẹ̀rẹ̀ sí ń wó
- Boko Haram sígun bo ìpínlẹ̀ Yobe, ikọ̀ ọmọogun òfurufú dojú ìbọn kọ wọ́n
- Babaláwo rí ẹ̀wọ̀n he! lẹ́yìn tó ṣe ìwòsàn fún obìnrin pẹ̀lu tábà fínfín, ló bá kú lójijì!
- ‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’