You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Ọwọ́ tẹ Sani fọganaisa tó fipá pọ́ ọ̀dọ́mọbìnrin ọdún 15 pa ní Gombe
Ọwọ ti tẹ Sani Sale, fọganaisa, ọmọ ọdun mejidinlogoji kan ni ipinlẹ Yobe to sa nle lẹyin to fipa ba ọmọbinrin ọmọ ọdun marundinlogun kan lo pọtọmọbinrin naa si ku si yara rẹ.
Ilu Gadaka ni ijọba ibilẹ Fika ni ipinlẹ Yobe ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe sọ, ni ọjọ kẹwaa, oṣu keji, ọdun 2021 ni ọmọdebinrin naa kiri akara lọ sigboro ṣugbọn ti awọn obi rẹ ko si ri i ko pada wale mọ titi ti ilẹ ọjọ naa fi ṣu.
Nigba ti ilẹ ọjọ keji mọ ni wọn ri oku rẹ ninu yara Sani Sale.
Ni kete ti aje ọrọ naa ṣi mọọ lori lo ti na papa bora lọ si ipinlẹ Gombe nibi ti ọwọ ọlọpaa ti pada wa tẹ ẹ.
- Agbaṣẹ́ṣe jẹ búlálà méjìlá lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀
- Ìrọ́ ní ò, a o fí ìgbà kankan fí Olupelumi Fagboyegun, Ìbátan Akeredolu sí ẹ̀wọ̀n- Iléẹ́jọ́ ìpínlẹ̀ Ondo
- Ọmọ Nàìjíríà Invictus Obinwanne Okeke rẹ́wọ̀n ọdún mẹwàá he l'Amerika lórí ẹ̀sùn jìbìtì $11m
- Wo àwọn ohun méje tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ngozi Okonjo-Iwealla àti ọkọ rẹ̀ Ikemba
- Wo ohun 10 tó yẹ́ kó mọ̀ nípà Ọ̀gà EFCC, Abdulrasheed Bawa tí ààrẹ̀ Buhari yàn