You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Ẹsẹ odù Ifa ló fi ṣúre fún ọmọ Nàíjíríà ní àyájọ́ ọdún tuntun
Adura lọtun losi, ni mu ẹmi ẹda gun.
Ọpọ ojo adura lo ti n rọjo sori awọn ọmọ Naijiria lati ileesẹ BBC Yoruba lati igba ta ti wọnu ọdun tuntun 2021.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Pásítọ̀ Adejare Adeboye rọ òjò àdúrà sórí ọmọ Nàíjíríà lọ́dún tuntun
- Bí 2020 ṣe ń lọ sópin, Alapinni Oosa wúre ọdún fún ọmọ Yorùbá
- A ti yí orin ọdún ń lọ sópin sí èdè Igbo àti Hausa - Mama Fasoyin
- Àkójọpọ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó dára àti èyí tó burú tó wáyé ní 2020
- Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká ọmọ Nàíjíríà tó jáde láyé lọ́dún 2020
- Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021
- Ẹ wo àwọn èèkàn eléré ìdárayá tó bá ọdún 2020 lọ
- Àwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 2020 pẹ̀lú ìtàn lórí bí wọ́n ṣe jáde
- Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ táwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run sọ nípa ọdún 2021
Nilana ti ibilẹ, Baba Awo, Oluwo Jogbodo Orunmila naa ree, to n rọjo adura sori awọn araalu gẹgẹ bii iwure ọdun tuntun.