South Africa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa
Wọn idalu ni iṣelu, bẹẹ gẹgẹ lọrọ ti ri pẹlu iyatọ to wa laarin aṣa ilẹ Naijiria ati ti orilẹede South Africa.
Awọn ọmọ Naijiria ti wọn fi orilẹ-ede South Africa ṣe ibuje ṣalaye pe ki ọlọjọ to de lawọn ọmọ ilẹ naa yoo ti maa fowo pamọ fun eto isinku wọn eleyi ti ẹnikan ko gbọdọ da iru laṣa lorilẹede Naijiria.
Wọn ni ibalopọ gan an ko jọwọn loju ati pe ọmọ ọdun mẹrinla le maa fẹnu ko ẹnu pẹlu ọmọ ọdun mẹrinla mii loju titi ti ẹnikan o si le sọ pe ki lẹ n ṣe ni bẹyẹn.
- Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO
- Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti
- Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò
- 'Àlàyé rèé lórí ìdí ti mo fi na ọmọ òrukàn, tí mo sì tì í mọ́ ilé ajá'
- Àwọn èèyàn ń san ìdámẹ́wàá tó "Heavy" fún mi ni mo fi ń r'áànú ṣe - Iya Adura Esther
- Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva
- Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun
Awọn ọmọ Naijiria to wa ni South Africa tun fikun ọrọ pe awọn ọmọ ilẹ naa kii saaba wọ aṣọ ibilẹ wọn nigba ti wọn ba n ṣe igbeyawo.