Cairo: Ilé oúnjẹ fáwọn Yorùbá ní Cairo, Egypt
Lẹ́yin ti ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ṣe aṣeyọri ti wọn gba lara awọn ami ẹyẹ bọ wale lati idije AFCON 2019 to waye lorilẹede Egypt, awọn nkan apawo wọle mii ṣi wa tawọn ọmọ Naijiria ń gbe ṣe lorilẹede naa.
Ile ounjẹ Yoruba yii jẹ ọkan lara iṣẹ ọwọ awọn ọmọ Naijiria to n gbe ni ilu Egypt.
Ko jọ bi ẹni pe kata kara ounjẹ tiwa n tiwa Yoruba lọhun nira fun wọn pẹlu ifọrọwanilẹnuwo akọroyin BBC Yoruba.
Koda wọọ wọọ lero maa n wọ lati wa jẹ ounjẹ Yoruba ni kete ti wọn ba ti ṣilẹkun titi di aago mejila oru.
Ṣugbọn bawo ni wọn ṣe ń ra iru, ewedu, ẹfọ Gure, Tẹtẹ ṣe ń rọrùn fun wọn bi wọn ṣe sọ?
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii
- Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington
- Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
- Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́...’ rèé
- Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ
- Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
- Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin