Coronavirus Cases in Africa: Ṣé lóòtọ́ọ́ nipé irọ́ n'ìjọba Nàìjíríà ń pa lórí ìtànkálẹ̀ ààrùn coronavirus?
Ṣe lootọọ ni pe ijọba orilẹede Naijira n parọ lori ajakalẹ aarun coronaviris?
Ọpọ ọmọ Naijiria lo gbagbọ pe irọ ni ijọba n pa lori ọrọ covid-19, wọn ni wọn kan fẹ fi ọrọ ajakalẹ aarun naa kowo jẹ ni.
Ẹ maa bawọn daṣa iru rẹ o, nitori otitọ ni pe aarun covid-19 wa ni Naijiria.
Ṣe lootọọ ni pe ijọba orilẹede Naijira n parọ lori ajakalẹ aarun coronaviris?
- Bí mo ṣe ṣẹ́gun Coronavirus rèé - Seyi Makinde
- Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko
- Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria
- Kí ló mú àwọn aládùúgbò Mọ́ṣáláṣí Alhaja kọlu àwọn ọlọ́ọpàá?
- Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan
- Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika
Ọpọ ọmọ Naijiria lo gbagbọ pe irọ ni ijọba n pa lori ọrọ covid-19, wọn ni wọn kan fẹ fi ọrọ ajakalẹ aarun naa kowo jẹ ni.
Ẹ maa bawọn daṣa iru rẹ o, nitori otitọ ni pe aarun covid-19 wa ni Naijiria.
Ijọba ṣi n tiraka lati oogun si aarun naa to fi di bi a ti ṣe n sọrọ yii.
Ajọ WHO ni titakete si ara ẹni lo ṣe pataki bayii lati dena aarun covid-19.