You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Ẹgbẹ ọmọ Yorùbá kí Gomina Abiola Ajimobi kú oríire ọjọ́ ìbí
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan, Central Council of Ibadan Indigenes(CCII) n ṣe akanṣe eto igbalejo fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mọkandinlaadọrin ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi.
Ile isẹ iroyin BBC lo ni awọn aworan yii.