BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ikọ Boko Haram
Ìjìyà tó bá tọ́ sí agbésùnmọ̀mí la máa fún ṣọ́jà tó bá ń dúró de àṣẹ kó tó pa wọ́n- Mínísítà ètò ààbò
10 Agẹmo 2026
0:59
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 0,59
10 Agẹmo 2026
Agbèsùnmọ̀mí pa ṣọ́já, dàná sun àgọ́ ọlọ́pàá, iléèwòsàn àti yàrá ìkàwé
9 Agẹmo 2026
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
8 Agẹmo 2026
"N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀"
6 Agẹmo 2026
Amẹ́ríkà kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kúrò ní Nàíjíríà, ohun tó fàá rèé
3 Agẹmo 2026
"Èyi ni ohun tí Olúwa sọ fún mi nípa ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso" – Pásítọ̀ Adeboye
30 Òkùdu 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérèégbè 'Operation Kosaye' tó gbérasọ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun
29 Òkùdu 2026
Sunday Igboho ṣàlàyé ipò tí òun àtàwọn ẹ̀ṣọ́ Iru Ẹkun tó farapa nínú ìkọlù Old Oyo National Park wà
29 Òkùdu 2026
Wo ohun tí òfin nọ́mbà ìdánimọ̀ tí Aarẹ ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lù túmọ̀ sí fún ọ
28 Òkùdu 2026
A ti bẹ̀rẹ̀ sí ni lo ẹ̀rọ 'Drone' fi maa ṣe ìwádìí àti dẹkun ìwà ọdaran nipinlẹ Eko-Ọlọ́pàá
19 Òkùdu 2026
Ìgboro dàrú n'Ilorin lẹ́yìn ìròyìn tó tàn kálẹ̀ pé àwọn agbébọn ti ya wọ àwọn ilé ẹ̀kọ́, ọlọ́pàá kìlọ̀
18 Òkùdu 2026
Òní ni ìdájọ́ àwọn afurasí agbésùnmọ̀mí tó lé ní 400 yóò wáyé l'Abuja
18 Òkùdu 2026
Àdó olóró agbésùnmọ̀mí ṣekúpa ọlọ́pàá mẹ́ta
17 Òkùdu 2026
Ṣé lóòótọ́ làwọn agbésùnmọ̀mí Lukarawa láti Apá Àríwá ti wọ inú igbó lọ l'Ogbomoso? Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo ti sọ̀rọ̀
15 Òkùdu 2026
Iléeṣẹ́ ọmogun dóòlà ìyàwó ọ̀gágunfẹ̀yìntì tó kú sí àkàtà àwọn jàndùkú agbébọn lẹ́yìn tí wọ́n sin ọkọ rẹ̀
15 Òkùdu 2026
Àjọ CAN kéde ọjọ́ òní gẹ́gẹ́ bíi ọjọ́ 'Àìkú Dúdú' láti dárò àwọn ọmọ Naijiria tó ń jìyà ètò ààbò tó mẹ́hẹ
14 Òkùdu 2026
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wa ló ti rẹ̀ sára àmọ́ inú wa dùn pé a gbòmìnira – Àwọn tó gba ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ Boko Haram
13 Òkùdu 2026
Yàtọ̀ sí June 12, àlàyé rèé nípa àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mẹ́fà míì tí kò bá ti sọ Nàíjíríà sójú ogun abẹ́lé
12 Òkùdu 2026
Agbébọn pa èèyàn mẹ́ta nílé ẹ̀kọ́, ọlọ́pàá, ológun, fijilanté dènà ìjínigbé, pa agbébọn kan
11 Òkùdu 2026
DSS lọgun pé àgbébọn fẹ́ kọlu iléẹ̀kọ́ l‘Edo, ìjọba ti iléẹ̀kọ́ mẹ́ta pa
11 Òkùdu 2026
Àṣírí abilékọ̀ tó jí ara rẹ̀ gbé, béèrè ₦50m owó ìtúsílẹ̀ tú, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ̀ ẹ́ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nílé ìtura
9 Òkùdu 2026
Oriyomi Hamzat ṣàlàyé àjọsẹpọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Sheikh Gumi, ìgbésùnmọ̀mí àti akatakítí ẹ̀sìn
6 Òkùdu 2026
Yinka Alaseyori ṣàlàyé ara rẹ̀ lórí fídíò tó ṣe nípa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
3 Òkùdu 2026
Page
1
nínú
12
1
2
3
4
5
6
7
12
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology