Kò ṣe á má gbọ̀ ọ́
Ẹyin oṣiṣẹ, ẹ mura fun iyanṣẹlodi alaini gbedeke
Ọjọ wo lo di agbẹnusọ awọn oṣiṣẹ?
Ẹgbẹ oṣiṣẹ Naijiria, NLC lo ma n sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ wọn lawọn ipinlẹ to ṣi n lọra lati san ilana owo oṣu tuntun alaadọrin ẹgbẹrun naira lati gbaradi
Ṣe pe ipinlẹ kan wa ti gomina ko i tii buwọlu owo yii?
NLC ni ipari oṣu yii ni gbedeke fawọn gomina ipinlẹ tọrọ kan
Jẹ ki n tete lọ soju opo bbc.com/yoruba lati mọ boya ipinlẹ mi wa lara wọn
Ihin ile ọhun ile
Lo difa fawọn ọmọ Naijiria mẹrin yii
Ti wọn dibo yan sipo oṣelu lorilẹede Amẹrika ati Australia
koda ọmọ Yoruba ni mẹta ninu wọn
Fauzia/Akinlabi, emi gan n wo orilẹede ti mo ti le lọ gbapoti o
ṣe o ti gbe tilẹ yi tan ni?
ẹwọn gbere ni mo fẹ fawọn afurasi ọlọpaa to ṣekupa ọmọ kan ṣoṣo ti mo bi o
Iya Sulyman Ayeyemi, akẹkọọ poly to kagbako iku lọwọ awọn ọlọpaa kan ni ipinlẹ kwara lo sọ bẹẹ
Alaye iroyin yii n bẹ loju opo bbc.com/Yoruba.
