Nítorí kí Aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí- Olagunsoye Oyinlola

Wo ọ̀nà àbáyọ mẹ́rin láti fi borí ogun Boko Haram ní Nàìjíríà- Olagunsoye Oyinlola

Oloye Olagunsoye Oyinlola ba BBC soro ni kikun lori ohu to ṣokunfa ogun Boko Haram ni ariwa Naijiria.

O sọ ohun ti oju rẹ ri ni Maiduguri lasiko to fi wa lẹnu iṣẹ ologun nibẹ.