Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
John Adewuyi, ẹni to jẹ arara, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, aye ti ro pe oun ko lee ri aya fẹ́, amọ oun dupẹ pe Ọlọrun fun oun ni aya rere, ti o n tọju oun daada.
Adewuyi ni ifẹ maa n tan isoro, ẹkun, pẹlu isẹlẹ aidaa to ti waye sẹyin, ti yoo si tun mu ayọ̀, ibukun ati igbega wọnu ile wa.
Ninu ọrọ ti aya rẹ, o ni kii se owo ni ọkọ oun fi fa oju oun mọra, tori inu yara kansoso ni o n gbe ti oun fi fẹ, ti ko si ni kẹkẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún
- Ebi yóò ti lu Nàíjíríà pa, tó bá jẹ́ PDP kò se dáadáa - Jonathan
- Ìjìyà síse ayédèrú isẹ́ onísẹ́ kò kún tó - Jide Kosọkọ
- Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀
- Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè
- Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
- Ebi sọ ìyá àgbà di awa kẹ̀kẹ́ Maruwa
O fikun pe inu oun maa n dun lati ba ọkọ oun rin ni titi, tawọn yoo si fa ara awọn lọwọ, bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan yoo maa fi ọwọ tọ̀ ara awọn lasiko tawọn ba n kọja ni popo.