Child Labour: Òbí mi kú nígbà ti mo wà lọ́mọ́ ọdún kan'
Emi ati ọrẹ mi la jọ n tọrọ owó fún ìyá àgbà -ọmọde
Fifi ọmọde ṣowo wọpọ ni ilẹ Afrika ṣugbọn tilẹ Naijiria lo pọ ju.
BBC Yoruba jade lọ ṣiṣẹ iwadii nipa ọrọ yii ni eyi ti o ti hande pe ko dun mọ awọn ọmọ ninu.
Ajọ iṣọkan agbaye to n risi ọrọ ọmọde ni agbaye UNICEF ni orilẹ-ede Naijiria lo ni ọmọde ti ko lọ sile iwe ti pọju lagbaye.
BBC ba ọmọde kan ti o sọrọ lori iriri rẹ bi oun ṣe n tọrọ owo.
O ni owo ti oun ba tọrọ yii ni oun ati iya agba maa jọ fi n jẹun.
O ni mẹnuba bi oun ṣe fẹ ko sọwọ oniṣekuṣe nigba kan.