Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Adajọ Olabisi Ogunkanmi ile-ẹjọ Majisireeti to wa ni Iyaganku nilu Ibadan,ti paṣẹ pe

ki wọn fi Olori Ọọni Ile-Ifẹ tẹlẹ, Naomi Silekunola ati Oriyomi Hamzat to jẹ alakoso ileeṣẹ redio Agidigbo pamọ sọgba ẹwọn.

Eyi ko ṣẹyin apejẹ ti Naomi ṣagbatẹru rẹ n'Ibadan nibi tọmọde marundinlogoji ti ku

Nigba wo n'igbẹjọ yoo tun waye?

Lo soju opo BBC Yoruba fun ẹkunrẹrẹ.

''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Mi o kabamọọ wi pe mo yọ owo iranwọ ori epo bẹntiroolu kuro

Aarẹ Bola Tinubu lo sọ bẹẹ nigba to n dahaun ibeere awọn akọroyin lalẹ ọjọ Aje

Koda Tinubu tun sọ pe oun ko ni wẹyin wo lori abadofin owo ori tuntun to wa niwaju ile aṣofin agba l'Abuja

Ẹkunrere wa lori ikanni BBC Yoruba

''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Eṣu laalu ogiri oko, o bẹlẹkun sunkun kẹrẹ o bẹlẹkun

Ṣebi kristẹni ni ọ, nigba wo lo bẹrẹ si bọ Esu?

Emi ma kọ, oni lawọn ọmọlẹyin Esu n ṣe ayajọ ọjọ Ẹṣu niluu Akure

Ti ẹ ba fẹ mọ bi ọdun Esu ṣe lọ lonii niluu Akure