You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Ijọba Naijiria, ẹ yọ orúkọ mi kúrò lára àwọn afurasí tí ẹ n wa
Sunday Adeyemo, Igboho lo sọ bẹẹ.
Igboho ni ibanujẹ lo jẹ foun boun ko ṣe lominira lati le rin kiri ni Naijiria
Iyoku iroyin ọhun wa loju opo wa
;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;;
"Aadọta ọdun loni, ìlànà oyè jíjẹ Ibadan ṣì máa dúró digbí.
Itumọ?
Gomina Seyi Makinde lo sọrọ yii nigba to ṣabẹwo si idile Olubadan to waja,Ọba Owolabi Olakuleyin
Makinde ni gbogbo Ibadan ti wa niṣokan bayii.
Nigba wo ni Olubadan tuntun yoo jẹ bayii
Kan soju opo BBC.Com/Yoruba fun ẹkunrẹrẹ iroyin
'''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''
Mo le ku nitori apo fulawa kan, kawọn ọmọ mi ṣaa ti ri ounjẹ jẹ
Haa ki lo le to bẹẹ, ko ma siku loju rẹ?
Emi kọ o, baba kan tawọn ọmọ rẹ ko jẹun fọjọ mẹrin ni Gaza lo sọ bẹẹ fun BBC
Ajọ UN ti fidi ẹ mulẹ, pe o ti le lẹgbẹrun kan awọn Palestine to ti ku bayii latari ebi
Ki wa nidi abajọ gan an?
Ti o ba fẹ mọ...ẹ kan si wa...