You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
2023 Nigeria Election: Ìgbàgbọ́ wa ní pé Nàìjíríà ṣì máa dùn lẹ́yìn ìdìbò ọ̀la yìí- Àwon olùgbé Nàìjíríà
Idibo yii naa lo le fun wa ni ayipada ti a n fẹ ni Naijiria, a maa dibo bo tilẹ jẹ pe ẹbi n pa wa.
Tẹlẹtẹlẹ nkan ko ri bayii rara ṣugbọn o ti wa le ju agbara wa lọ bayii
A ko ri owo na, ebi n pa wa ṣugbọn sibẹ-sibẹ a ṣetan lati dibo fun e\ni to maa mu igab ọtun de ba Naijiria.
- Ṣé o lè dìbò fún olùdíje obìnrin? #BBCNigeria2023
- Gbajúmọ̀ Òṣèré apanilẹ́rin Sisi Quadri pàdánù ìyà rẹ̀, omijé bọ́
- Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ wákàtí, Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Finland tú adelé olórí IPOB, Simon Ekpa sílẹ̀
- Ẹ gba kámú lórí ẹni tí INEC bá kéde pé ó wọlé, àlááfíà Nàìjíríà ni mo fẹ́- Buhari
- Mọ̀ síi nípa ewu tó rọ̀ mọ́ níní ìbálòpọ̀ lásìkò ìlóyún lórí ètò Sé lóòtọ́ ní BBC
BBC Yorùbá jáde lọ bèèrè bóyá àwọn eèyàn máa gba owó lọ́wa ẹni tó ba fẹ́ ra ìbò wọn?
Opọlọpọ lo sọ pe awọn ko ni ta ibo awọn rara nitori pé awòn ko ni fẹ ki iay tun jẹ awọn.
Awọn mii sọ pe koda ki awọn agba owo lọwọ awọn oloṣelu, ẹni to wu awọn lawọn ṣi maa dibo fun lasiko idibo.
Opọ \moọ Naijiria lo gabdura fun alaafia ati isinmi léyin idibo ọla yii pe didun ni ọsan a so laṣẹ Olodumare.