You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Ekiti 2022: Fayemi ni Bàbá ìsàlẹ̀ gbogbo APC ni Ekiti, kìí ṣe fún èmi nìkan- Abiodun Abayomi Oyebamiji
Ogbeni Abiodun Abayomi Oyebamiji ni ẹgbẹ All Progressives Congress kede pe yoo ṣoju wọn lati dije du ipo gomina ipinlẹ Ekiti.Ta ni Abiodun Oyebamiji tí APC dìbò yàn bí olùdíje gómìnà l'Ekiti
Oyebamiji ni awọn mii pe ni oludije ti gomina Fayemi to n tukọ ipinlẹ Ekiti bayii fami ororo yan.
Bẹẹ naa ni oun funra rẹ si sọ fun BBC pe Fayemi kii ṣe baba isalẹ fun oun nikan rara bikoṣe fun gbogbo ol;oselu APC ni Ekiti pe fun idi eyi kii ṣe pe oun nikan ni Fayemi fọwọsi.
O menuba koko mẹrin ti Fayemi n beere lọwọ ẹnikẹni to ba fẹ gba ipo lọwọ rẹ ninu ididbo gomina ódun yii.
- Àwọn ọmọbìnrin oníwọ́kuwọ́ ló mú kí ń yẹ̀bá nídìí iṣẹ́ tíátà
- Abdulsalami ní kò sẹ́ni tó pa MKO Abiola, àìsàn ló pa á, ẹbí Abiola yarí
- Bí ayẹyẹ ìsìnkú Alao Akala yóò ṣe lọ rèé
- Ọmọ Nàíjíríà, ẹ yé yan àwọn ‘Grandpa’ ní ààrẹ, ẹ wá ọlọ́gbọ́n ọ̀dọ́ tó tún sán-an-gun - Seyi Makinde
- Àwùjọ àgbáyé, ẹ ṣèrànwọ́ fún Burkina Faso kó le borí ìṣòro - Olórí ìjọba ológun
- Tiyín lẹ ṣe o, àwa kò gbà èsì ìdìbò abẹ́nú PDP l‘Ekiti - Segun Oni
Bakan naa ni Oyebamiji menuba awọn igbesẹ ti ẹgbẹ yoo gbe lati bori wahala to wu ko wa nilẹ lẹyin ididbo ẹgbe APC ni Ekiti to kọja yii.
O tun ni ẹgbẹ naa ko le daru ni Ekiti
- Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii
- Mọ̀ sií i nípa Oba Yesufu Asanike , Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba
- Àwọn Oba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí Oba míràn jẹ lójú ayé wọn
- 'Àǹfàní ńlá ni BBC fún wa'
- Wo Mẹkáníìkì alápá kan tí ayé ń pariwo pé o mọ ìjánu ọkọ̀ ṣe púpọ̀
- Wo bí wọ́n ṣe sin Ọba Satani pẹ̀lú ọkọ̀ àti orin tó fẹ́ràn jù