You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
BBC Nigeria 2019: Ọ̀rọ̀ àwọn olóṣèlú, tásìkò bá tó, akólòlò á pe baba - Bode George
O ti pẹ ti ọrọ ti n jẹyọ si gbangba laarin oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ àti aarẹ Muhammadu Buhari, Ni kete ti ọkan ba sọ ni ẹnikeji yoo ti fesi. Gẹgẹ bi agba oloṣelu ti awọn mejeeji jẹ, iwoye yii ni Oloye Bode George fi fi ọrọ agba ba wọn sọrọ nitori Yoruba ni agba la fi n wagba.