Fayemi: Àwọn àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè níbi ìbúra

Awọn awọran to joju ni gbese nibi ayẹyẹ iburawọle sipo Fayemi ni Ado Ekiti

Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan n duro ki ayẹyẹ naa bẹrẹ
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Awọn lọbalọba ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Oni nkan laa jẹ o ṣẹ e .Fayemi balẹ biba sibi ayẹyẹ iburawole
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Awọn Imamuu wa nibẹ lati fi adura ran ijọba tuntun yi lọwọ
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Ko si ayẹyẹ iburawọle ti ko ba si adajọ ti yoo bura fun Gomina tuntun
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Ogbeni Kayode Fayemi ati iyawo rẹ ni wọn jijọ kọwọrin wa ibi ayẹyẹ naa
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Ki lẹ lero wi pẹ alagba Bisi Akande n sọ fun alaga ẹgbẹ APC teleri alagba John Odigie-Oyegun?
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja osere Odunlade Adekola naa peju sibi ayẹyẹ naa
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Igbakeji Gomina Otunba Bisi Egbeyemi ati Iyawo rẹ n yọ sẹṣẹ
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Eko Akinwumi Ambode naa yọju
Aworan iburawọle fun Kayode Fayemi
Àkọlé àwòrán, Babajide Sanwoolu naa wa ba Kayode Fayemi yọ