World Cup 2018: Ahmed Musa di ààyò ní Naijiria

Oniruuru aworan Ahmed Musa ni awọn ọmọ Naijiria ya si ara nkan ni orisirisi.

Amed Musa lara iwe ipolongo ibo

Oríṣun àwòrán, @Phillip

Àkọlé àwòrán, Bi eegun ẹni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ. Awọn ọmọ Naijiria n pe Ahmed Musa ko wa jẹ aarẹ Naijiria
Ahmed Musa

Oríṣun àwòrán, @bukolamainassara

Àkọlé àwòrán, Naijiria fun Musa ni tikẹẹti lati dije du ipo Aarẹ lọfẹ lori ayelujara
Ahmed Musa

Oríṣun àwòrán, @FIFAWorldCup

Àkọlé àwòrán, Ahmed Musa di aayo agbabọọlu tawọn ọmọ Naijiria n wari fun
Apo irẹsi pẹlu aworan Amed Musa

Oríṣun àwòrán, @Concaholic

Àkọlé àwòrán, Ahmed Musa lawọn ọmọ Nigeria ri bii Olugbala ni gbogbo ẹka
Apo irẹsi pẹlu aworan Ahmed Musa

Oríṣun àwòrán, @Phatill

Àkọlé àwòrán, Koda awọn ọmọ Naijiria tun wwe Lawani fun Ahmed Musa gẹg bii alasẹ wọn
Ọwọ ti faanu ge

Oríṣun àwòrán, @dhe_Mechanic

Àkọlé àwòrán, Ọkunrin yii ni Ahmed Musa lo jẹ ki faanu ge oun lọwọ nigba to fo soke nitori ayo ti Musa gba wọle
Ọkunrin kan yọ ikun silẹ

Oríṣun àwòrán, @Can_caworm

Àkọlé àwòrán, Saaju idije Super Eagles pẹlu Iceland ni ọkan awọn ọmọ Naijiria ko ti balẹ, wọn n gbadura si Ọlọrun ko ko awọn yọ
Amed Musa lara iwe ipolongo ibo

Oríṣun àwòrán, @Phillip

Àkọlé àwòrán, Bi eegun ẹni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ. Awọn ọmọ Naijiria n pe Ahmed Musa ko wa jẹ aarẹ Naijiria