You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Okafor Nkechi Agness: Ẹbí kọ̀ mi sílẹ̀, Bàbá mi kú lórí wàhálá mi ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti tọrọ bárà
Omọ Igbo ni mi ṣùgbọn Ekiti ni wọn bi mi si ni mo fi gbọ ede Yoruba daadaa.
Okafor Nkechi Agness lo gbalejo BBC Yoruba nibi to ti ri oore ọfẹ lati sọ nipa irinajo aye rẹ lati kekere.
O sọ nipa ala rẹ lati ṣoju Nijiria ninu idije ere sisa gbogbo lati kekere rẹ ko to di pe o ṣaisan nigba kan ti ẹsẹ si kọ alti ṣiṣẹ mọ.
O ṣalaye ohun ti oju Obi rẹ ri ki Baba rẹ to re ibi agba n re ati ibi ti ọrọ rẹ de duro.
Agness sọ bi oun ṣe ronu lati pa ara oun ni akoko kan ki aanu Olodumare to sọrọ lori aye oun.
O gba awọn to ni ipenija kankan ni ara wọn ni iyanju lati maṣẹ gbe igba bara ṣugbọn ki wọn ni afojusun ot dara ati oju inu lati wadi talẹnti ti Olodumare fi jinki koowa.
- Wo àkójọpọ̀ ìlérí táwọn olùdíje gómìnà l‘Oyo ṣe fáráàlú níbi ìpàdé ìta gbangba BBC Yorùbá
- "Ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń gbé ní Eko, Ibadan, Osogbo ló ti kú..."
- O ní ìdí tí mo fi yan ilé Olórogún Ooni Ife dípò ilé ọlọ́kọ kan- Olori Tobi Phillips Ogunwusi
- Ìtàn bí Egúngún Olóòlù ṣe wọ Ibadan àti ìdí tí obìnrin kìí fi ṣíjú wò ó
- Ọdún méjìlá la fi gbé nínú ṣọ́ọ̀bù tí à n wẹ̀ lórí gọ́tà nídájí kí a tó rí àánú gbà- Son of the Prophet
- Ẹ wo Motiriolaoluwa ẹni ọdún mẹ́rin tó n fi ìlù dára bíi àgbàlagbà
- Wo àṣírí bí àwọn 'influencer' ṣe ń gba owó lọ́wọ́ àwọn olóṣèlú láti tako ẹgbẹ́ òṣèlú míì
- Iya Ibeji kò rántí ńkankan mọ́, ẹnu ti wọ́ sí ẹgbẹ́ kan- Omo Iya Ibeji ọmọ araye le