You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Yemi Elesho, ìlúmọ̀ọ́ká adẹ́rínpòṣónú jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí 'Ṣé o láyà?'
Ilumọọka adẹrinpoṣonu ni Yẹmi Ẹlẹṣọ, amọṣa lori eto Se o laya tosẹ yii, o da bẹbẹ pẹlu awọn ibeere wa gbogbo.
- Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
- Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn
- Lóòótọ́ lòògùn owo wà ṣùgbọ́n ayédèrú aláwo ló ń lo ẹ̀yà ara -Ẹlẹ́búìbọn
- Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla
- Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo
- Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé Peter Fatomilola ni 'Papa Ajasco' àkọ́kọ́?
Ibeere loriṣiriṣi ni o dojukọ lori eto tọtẹ yii, bi o tilẹ jẹ wi pe ẹnu yii naa ko jẹ ki Yẹmi o gbadun sibẹ, o jẹwọ ara rẹ pe ẹnu nikan kọ loun ni o, oun mọ nipa aṣa ati iṣe Yoruba daadaa.