Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lójú mi ní àhámọ Saudi

Oṣu mẹ́rin ni Zainab Aliyu lo ni ahamọ ni orilẹede Saudi Arabia to n reti iku lẹyin ti wọn fẹsun kan pe o gbe oogun oloro wọ orilẹede naa.

Ijọba orilẹede Naijiria ṣe iwadi to fi han wipe awọn janduku oṣiṣẹ papakọ ofurufu to wa ni Kano lo gbin oogun oloro naa sinu apo rẹ. Ijọba Naijiria si fi eyi to ijọba Saudi leti ti wọn fi da ọmọ obinrin naa silẹ.

Ninu fidio yii, oo ṣalaye fun BBC oun toju oun ri ni ahamọ.

Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: