BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Àwọn àwòrán tó gbayì láti Ojúdé Ọba
23 Ògún 2018
Ẹ fójú lóúnjẹ níbi ayẹyẹ Ojúdé Ọba ti ọdún 2018 tó ńwáyé lọ́wọ́lọ́wọ́ ní Ijẹbu Ode
Àkọlé àwòrán,
Ẹlẹ́gbẹ́ ń jẹgbẹ́ gbé àṣà Yorùbá ga pẹ̀lú aṣọ wọn
Àkọlé àwòrán,
Ẹlẹ́gbẹ́ ń jẹgbẹ́ gbé àṣà Yorùbá ga pẹ̀lú aṣọ wọn
Àkọlé àwòrán,
Ojúdé Ọba 2018: Asọ ń pe asọ ránsẹ́
Àkọlé àwòrán,
Ibi ìgbàlejò ìtagbangba fún Ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Olóyè ilẹ̀ Ijẹbu lórí ẹṣin
Àkọlé àwòrán,
Àwọn aṣọ ìbílẹ̀ ń ṣẹ́yọ lẹ́lẹ́gbẹ́ ńjẹgbẹ́
Àkọlé àwòrán,
Awùjalẹ̀ ti ìlú Ijẹbu, Ọba Sikiru Adetọna níbi ayẹyẹ Ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ t'ọba làṣẹ Akilẹ-Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Àwọn Sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà kò gbẹ́yìn níbi ayẹyẹ Ojúdé Ọba
Àkọlé àwòrán,
Gígun ẹṣin náà kò gbẹ́yìn lára ètò fún ayẹyẹ Ojúdé Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ẹlẹ́gbẹ́ ń jẹgbẹ́ gbé àṣà Yorùbá ga pẹ̀lú aṣọ wọn
Àkọlé àwòrán,
Olóyè Balogun Alatishe ti ilẹ̀ Ijẹbu yan kiri lórí ẹṣin
Àkọlé àwòrán,
Ọ̀túnba Túnwàṣe tó tún jẹ́ alákoso ilé ifowópamọ́ FCMB àti ìyàwó rẹ̀
Àkọlé àwòrán,
Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, Bukola Saraki dé síbí ayẹyẹ náà
Àkọlé àwòrán,
Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye náà wà níkàlẹ̀
Àkọlé àwòrán,
Ìwọ́de ìdílé Kuku ní Ojúdé Ọba
Àkọlé àwòrán,
Egbẹ́ Bobagbinmo obìnrin Akile ijebu lọ kí Oba Awujale kú ìkàlẹ̀
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology