Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe

Àkọlé fídíò, Sàká: Oun ti orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe

Gbajúgbajà òṣèré tíátà, Afeez Ayétòrò tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Sàká ṣàlàyé nínú ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC wí pé oun ti orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe.

Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: