You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Independence Day Nigeria: Ọ̀kọ̀ọ̀kan àwòrán mẹ́fà yìí ló dúró fún ọdún mẹ́wàá ìtàn ilẹ̀ wa
BBC Se akojọpọ itan nipa Naijiria pẹlu aworan mẹfa pere, eyi to n salaye awọn igba manigbagbe ninu ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira.