Independence Day Nigeria: Ọ̀kọ̀ọ̀kan àwòrán mẹ́fà yìí ló dúró fún ọdún mẹ́wàá ìtàn ilẹ̀ wa

BBC Se akojọpọ itan nipa Naijiria pẹlu aworan mẹfa pere, eyi to n salaye awọn igba manigbagbe ninu ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira.