Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ile ifowopamọ agba Naijiria, CBN, tun gbe tuntun de ?

Ki ni wọn tun ṣe ?

CBN sọ pe ẹgbẹrun lọna ọgọrun-un naira ni gbedeke owo teeyan le gba lojumọ lori POS

Uhnnn?

Bakan naa ni awọn oni POS ko le san ju miliọnu kan ati igba naira lọ lojumọ

Ki wa ni wọn lo de ninu airowo gba yii?

Iyoku iroyin wa ni bbc.com/yoruba

................................................................................................................................................

Gomina ipinlẹ Osun, Ademola Adeleke ti paṣẹ itusilẹ Segun Olowookere, ọdmọkunrin ti wọn dajọ iku fun nitori poji adiyẹ

Ọdun 2010 ni awọn ọlọpaa mu Segun ati awn mii nigba to wa lọmọ ọdun mẹtadinlogun

...................................................................................................................................................

Ko din ni mọde kan to ku nibi apejẹ ipari ọdun ti olori Ooni tẹlẹ, Naomi Ogunwusi ṣe niluu Ibadan

Ikunle abiamọ o

Iroyin sọ pe akọlukọgba ṣẹlẹ, awọn eeyan tẹra wọn pa lai pẹ ti eto bẹrẹ ljọru

Nibo lo wa de duro bayii

Ẹkunrẹrẹ wa ni bbc.com/yoruba