You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Ẹlẹ́wọ̀n: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti kàwé yege ní ìdánwò Jamb
Ẹlẹ́wọ̀n kan ti ní inú ọgbà ni òun ti s‘orí rere nítori ibẹ̀ ni òun ti kàwé yege ìdánwò Jamb.
O ní nínú àwọn ẹlẹ́wọ̀n méjìlá táwọn jọ se ìdánwò náà, òun ni òun léwájú gbogbo wọn pẹ̀lú máákì 248.
Ẹlẹ́wọ̀n náà ní isẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ ni òun fẹ́ se, tó sì bẹ̀bẹ̀ fún ìsíjú àánú woni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Àṣìta ìbọn ọlọ́pàá ba akẹgbẹ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé ìyàwó, ikú dé!
- Oluwo: Ààrẹ Buhari, ẹ dájọ́ ikú fún gbogbo ẹni tó ń gbé òògùn olóró, agbésùnmọ́mi àti afinisoogun owo
- Irọ́ ni Tinubu ń pa o, PVC kìí parí iṣẹ́ – INEC
- Ẹlẹ́ṣin tó gbé òkú Ọba Wukari pọ̀n wọ inú igbó rèé o! Ó sọ ìrírí rẹ ó sì tún já irọ ìròyìn orí ayélujára nípa rẹ̀
- Wo bí ọ̀rẹ́ mẹ́rin tí wọ́n jígbé ni Ibadan sí Eko ṣe gba òmìnira lẹ́yìn owó ìtúsílẹ̀ láì sí ìrànlọ́wọ́ ọlọ́pàá