Nigerian Labour Congress: Diẹ rèé nínú àwòrán ìwọ́de àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Nàìjíríà ní Abuja, Eko àti Ibadan

Ohun tawọn oṣiṣẹ lawọn fẹ ni pe ki ile aṣofin ma gbe aṣẹ sisan owo oṣu kuro ni abẹ ijọba apapọ lọ si abẹ aṣẹ ijọba ipinlẹ.