You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀
Iwadi BBC fihan pe, eewọ ni fun alaboyun ni ilu Manfe Dove, lorilẹede Ghana lati bimọ tuntun sinu ilu naa.
Ti alaboyun ba si n rọbi, inu irora ni wọn yoo ti gbe jade lọ si ilu miran lati lọ bimọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
- Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
- Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
- Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
- Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde
- 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ'
- Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Nigba to n ba BBC sọrọ, Hanna Kosinah to diwọ-disẹ sinu salaye pe, oju oun ri mabo, ki oun to ri ọkọ ti yoo gbe oun lọ si ilu miran, lasiko ti oun n rọbi lati bi akọbi oun.
Agba ilu kan, to fi idi eewọ naa mulẹ ni, ohun kan lo fọ lati ọrun si awọn baba nla awọn pe awọn ko gbọdọ bi ọmọ, sin oku tabi ẹran sinu ilu naa, tori ilu mimọ ni.