You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Oba Adewumi Ogunleye: Nítorí ìfẹ́ ìlú àti ọ̀dọ́ ni mo ṣe padà sílé ẹ̀kọ́- Oba Towulade
Pínpín ọrọ̀ Naijiria lọ́gbọọgba ni ọna abayọ si iṣoro wa kìí ṣe ki a pin lọtọọtọ- Oba Ogunleye
Kabiesi Towulade ilu Akinhale ni ipinlẹ Ogun gba BBC Yoruba lalejo.
Nibẹ ni Oba Adewumi Ogunleye ti sọ ohun ti oju rẹ ri ko to fi agba ara pada silẹ ẹkọ.
Nibẹ lo ti kọ iṣẹ amofin to si lọ si 'Law School' to tun ṣe aṣeyege.
Oba sọ bo ṣe tori ifẹ ilu ki oun le maa ṣe idajọ ododo to tun pada lọ gab oye sii titi dori ọmọwe nipa iṣẹ amofin.
- Ṣé lóòtọ́- Bóo bá ń mu Garri jù tí wọ́n tàn ẹ́ pé ojú dídùn ni yóò gbẹ̀yìn rẹ; gbọ́ òótọ́ lẹ́nu onímọ̀
- Àwọn ọ̀rẹ́ mi lè fún mi ní 'One, one million' àwọn ọ̀rẹ́ ti yín ń kọ́? Kie kie ti sọ̀rọ̀sókè fún BBC Yorùbá
- Ìdásílẹ̀ ìpínlẹ̀ Ijebu ni àwa ń fẹ́, Yorùbá Nation kò ì tíì kàn wá - Ọba Adenugba
- Ká sọ pé mi kò díje, n kò lè dìbò fún Obi àti Atiku nítorí pé wọn kò kúnjú òṣùwọ̀n tó- Tinubu
- Bàbá mi Alafin Oyo fẹ́ràn ipa tí mo kó nínú Sinimá Anikulapo, wọ́n sì fẹ́ wò ó àmọ́... - Adedoja Alaafin
- Aya àti ọ̀rẹ́ kọ̀ mí sílẹ̀ lẹ́yìn ti mo pàdánù ẹ̀sẹ̀ mi ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti ṣagbe ni mo ṣe padà síṣẹ́ wẹ́dà- Yussuf
Oba Towulade gba awọn ọdọ Naijiria ni iyanju pe ibẹrẹ kii ṣe oniṣẹ ati pe ko si igba ti a daṣo ti a ko rilẹ fi wọ.
- Mọ̀ sí i nípa Oba Yesufu Asanike, Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo
- Mọ̀ síi nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ ríru tó mú ẹ̀mí 16,000 èèyàn lọ tó sì ba dukia $206b jẹ́
- Àwọn Oba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí Oba míràn jẹ lójú ayé wọn
- Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo
Bakan naa lo sọrọ lori iyapa ni Naijiriia pẹlu imọran fun awọn adari Naijiria pe ki wọn fi ootọ pin ọrọ Naijiria ki ọkan koowa le bale.
- BBC kéde orúkọ àwọn obìnrin tí wọ́n làmìlaaka jù lágbàyé lọ́dún 2022
- Èmi ní mo fún Afeez Abiodun ní orúkọ 'Ọwọ' tó ń jẹ́ -Yemi My Lover
- Kí ló fàá tí àwọn olóṣèlú kò fi ń lo àwòrán Buhari lórí ìwé ìpolongo ìbò wọn làsíkò yìí-
- Iṣẹ́ òpùrọ́ ni Olọ́run fi rán APC, wọn kò ṣiṣẹ́ ìlú kankan ní Kwara- Bolaji Abdullahi
- Láàrín Adeleke àti Oyetola, ta ló ń parọ́ lórí ọ̀rọ̀ N76 bílíọ̀nù, gbèsè owó oṣù òṣìṣẹ́ Osun-